Wahala niluu Etire: Won ni Kabiyesi ran agbanipa sawon ti
Transkript
Wahala niluu Etire: Won ni Kabiyesi ran agbanipa sawon ti
E ba wa dele E mo nipa wa ba wa sise Adiresi wa E polowo oja yin AKEDE Agbaye Idanileko ALAROYE Bi o ba fe Awon Iroyin to se koko Wahala niluu Etire: Won ni Kabiyesi ran agbanipa sawon ti won jo n ja sile Egbe APC wole de: Olawale Ajao, Ibadan ati Johnson Akinpelu, Abeokuta Nnkan daru mo PDP O lowo ·joô buruku kan ti ko sôee gbagbe boôroô loôjoô Aiku, Sannde, oôjoô karun-un, osôu karun-un, oôdun yii, jeô fun idile kan ti woôn n pe ni Oôtaniyi, niluu Etireô, nijoôba ibileô Waterside, nipinleô Ogun, peôlu bi awoôn agbanipa sôe ka woôn moôle laleô oôjoô naa, ti woôn sôa olori idile oôhun, Oôgbeôni Tajudeen Oôtaniyi Temidire ladaa titi ti oômoô ika oôwoô eô meji fi ja boô leôyin ti woôn ti fi ada ge oôkan ninu awoôn oômoô baba naa leti soônu, ti woôn si lu obinrin ile oôhun kan lalubami. O·roô ileô la gboô pe o fa yanpoônyanrin oôhun. Woôn ni oôba ilu naa, Eletireô tilu Etireô, Oôba Musa Adeniyi Adetokunboô, gbeôseô le gbogbo ileô to wa niluu yii, o ni idile kankan ko leôtoôoô lati ta ileô ti woôn jogun loôwoô awoôn baba-nla woôn nitori ti oôba ni ileô ati eôkun reô. Ohun tawon agbanipa sowo Eyi lo fa a ti awoôn idile kan fi gbena woju Oôba naa peôlu bi okunrin naa da ree woôn sôe pe e leôjoô si kootu, woôn ni kile-eôjoô gba awoôn loôwoô eô nitori o feôeô fi oôwoô oôla gba awoôn loju ni. Lara awoôn to pe Kabiyesi leôjoô yii ni idile Oôtaniyi yii. Loôjoô Aiku, Sannde, oôjoô karun-un, osôu karun-un, oôdun yii loôroô ileô naa gba oôna mi-in yoô fun idile Oôtaniyi, nigba ti woôn deede gbalejo ogunloôgoô awoôn janduku kan ti eônikeôni ko moô iye woôn. ALAROYE gboô pe marun-un ninu awoôn eeyan yii lo woô inu ile toô awoôn onile loô peôlu aake, ada, oôbeô atawoôn ohun ija oloro mi-in, ti woôn si beôreô si i kun awoôn oômoô eeyan bii eôni kun eôran okete; bi woôn sôe n ge woôn leti ni woôn n reô woôn leti soônu lai besôu-beôgba. Yatoô si bi woôn sôe fi oôgbeô ada ba gbogbo ara Alhaji Temidire jeô yannayanna, meôjoô ninu ika oôwoô eô lawoôn alailaaanu eeyan naa tun fi ada ge soônu ti baba naa si sôubu luleô, to daku gboônrangandan sinu agbara eôjeô ara eô to n sôan nileô. Bakan naa la gboô pe awoôn afurasi agbanipa oôhun fi ada ge eti oômoôkunrin eôni oôdun moôkanlelogun kan ti woôn n pe ni Niyi ja boô sileô, to sôe pe woôn ran eti oôhun moô agbari eô pada ni. Oômoô aburo Oôgbeôni Temidire ni Niyi yii, oôdoô eôgboôn baba eô ti woôn sôe lesôe yii lo n gbe nitori iya eô ti jade laye. Boya oôrun alakeji loôkunrin onisôowo ti woôn fi ada sôe nisôekusôe yii iba wa bayii bi ko ba sôe ti awoôn oôloôpaa ti woôn tete de leôyin ti awoôn ara adugbo naa kegbajare loôoô ba woôn. Awoôn agbofinro la gboô pe woôn gbe awoôn mejeeji ti woôn sôe loôsôeô loô sileewosan. Oôjoô keôrin ti Oôgbeôni Temidire beôreô si i gba itoôju ni woôn lo too ji saye, bo tileô jeô pe ileewosan oôhun naa lo sôi wa to n gba itoôju titi di asiko ti a fi pari akojoô iroyin yii. Loôjoô naa ni ALAROYE gboô pe awoôn agbofinro ti beôreô iwadii woôn lori isôeôleô oôhun, ti woôn si ti mu marun-un ninu awoôn ti woôn fura si pe woôn sôisôeô ibi naa. Akoôroyin wa pe Alhaji Temidire lori eôroô ibanisoôroô reô nileewosan to wa, ohun toôkunrin eôni oôdun mejileloôgoôta naa soô ree, “Eôbi wa lo pe Oôba leôjoô, emi kan jeô oôkan ninu awoôn eôbi yeôn ni, Alagba Akinoôla Alaba to jeô olori eôbi wa gan-an lo pe Oôba Adetokunboô leôjoô. Sôugboôn baba yeôn ti ku bayii, o ku loôjoô keôrindinloôgboôn, osôu keôfa, oôdun yii. Ironu oôroô temi naa lo pa a nigba ti awoôn eeyan yeôn sôe mi lesôe ti mo ba a soôroô lati oôsibitu ti mo wa yii nigba naa. Mo wa nile laleô oôjoô karun-un, osôu karun-un, oôdun yii, ni nnkan bii aago meôwaa aleô ni woôn de. Mo ti sun, awoôn aburo mi meji kan, Alaba Oôlayinka ati Tayelolu Oôtaniyi la joô jeôun aleô oôjoô naa. Leôyin ta a jeôun tan lemi woôle loôoô sun ni nnkan bii aago meôsan-an. “Emi ti sun loô ni temi ki n too Omoose Aregbesola soko oro s’Omisore lori eto isuna Osun Wahala niluu Etire: Won ni Kabiyesi ran agbanipa sawon ti won jo n ja sile Idibo 2014: Isokan yoo pada sinu egbe PDP Ekiti laipe—Adeniran Eedi ree o! Nitori apoti, iyaale ile fi obe gun obinrin egbe e pa n'Ijora Kayeefi! Oga ileewe ku sori irun n'Ilorin, lawon eeyan ba ni oninuure ni E tun pade wa lori ero E wa awon iroyin wa gboô ariwo, ‘Yee, o pa mi o’, ni mo ba sare jade. Bi mo sôe jade soôwoô awoôn eeyan yeôn niyeôn, ni woôn ba da ada bo mi. Mo sa woô ile igboônseô, woôn le mi woôbeô, woôn sôa mi ladaa moôbeô, woôn tun gbe mi woô yara iyawo mi, woôn tun beôreô si i sôa mi ladaa moôbeô. “Aburo mi kan sa gun oke aja loô ni tieô. Feyisôara to jeô iyawo eô, nisôe ni woôn de e lokun loôwoô mejeeji seôyin ti • Alaaji Tajudeen Temidire tawon agbanipa tun se lese niyi woôn si da oju eô boleô ninu yara eô. Woôn waa ko gbogbo eôru to ko sabeô beôeôdi peôlu awoôn iwe ileô ti mo ko si yara eô. Leôyin eô ni woôn pada wa si yara oôdoô mi, woôn ko Cefa (owo orileô-ede Benin) ti mo ko pamoô sinu ile. “Inu agbara eôjeô mi ni mo wa ti mo ti n japoro iku. Nigba ti woôn gboô ti mo mi kanleô ni woôn too fi mi sileô. Awoôn oôloôpaa ni woôn waa gbe mi loô sileewosan ijoôba to wa loôdoô wa. Nigba ti woôn koô mi nibeô ni woôn gbe mi loô si oôsibitu ijoôba ipinleô Ogun, woôn tun koô mi nibeô naa, leôyin iyeôn ni woôn gbe mi loô sileewosan aladaani ti mo wa ti mo ti n ba yin soôroô yii. “Woôn ti pa mi tan ko too di pe Oôloôrun ji mi saye. Oôjoô keôrin ni mo sôeôsôeô n beere pe ibo ni mo wa. “Alejo lo poô ju ninu awoôn ti woôn wa yeôn, sôugboôn mo da meôrin moô ninu woôn. Meôta ninu woôn jeô oômoôoôba, oôkan jeô oômoô eôgboôn eô, nigba ti awoôn meji yooku jeô oômoô bibi inu eô gan-an.” Ni ibamu peôlu ibeere akoôroyin wa, oôkunrin eôni oôdun mejileloôgoôta naa dahun pe, “O·moôbinrin mi kan lo sa jade lasiko ti woôn n na mi to pariwo seti awoôn araadugbo. Mi o waa moô bi woôn sôe sôe e ti woôn fi fi to awoôn oôloôpaa leti.” Nigba to n ba oôkan ninu awoôn akoôroyin wa soôroô, oômoô baba ti woôn koôlu yii, Omidan Oôtaniyi Oôlajumoôkeô Temidire, sôalaye pe baba oun ati Oôba ilu Etireô, Oôba Musa Adetokunboô Adeniyi ni woôn n ja sileô, ati pe nitori eô ni Kabiyesi sôe ran awoôn agbanipa si baba oun. Gege bo sôe soô, “O yeô ka loô si kootu lori eôjoô to wa lori oôroô ileô ti a n ja si yeôn loôjoô keje, osôu karun-un, oôdun yii, sôugboôn nigba ti oôjoô to yeô ka loô si kootu ku oôtunla, iyeôn loôjoô karun-un, osôu yeôn, ni woôn waa ka wa moôle. Latigba yeôn ni baba mi ti wa nileewosan fun itoôju titi doni. “Yinka Adeniyi to jeô oômoô eôgboôn Kabiyesi yeôn lo koôkoô koôja loô niwaju ile wa, o ba awoôn eôgboôn mi nibi ti woôn ti jokoo, sôugboôn woôn ko bi i leere nnkan to n wa laimoô pe nisôe lo koôkoô waa wo oju ileô na ki awoôn eeyan eô to n boô leôyin le moô asiko ti woôn maa sôisôeô ibi woôn. “Leôyin naa ni aburo Oôba kan tun wa si adugbo wa laleô oôjoô yeôn, o waa gbe moôto sitosi ile wa, o fi kaseôeôti orin sinu redio to wa ninu oôkoô oôhun. O waa yin orin yeôn soke laalaalaa kiyeôn le bo gbogbo oôroô ti awoôn eeyan ba n soô nile wa moôleô, nitori ki awoôn eeyan ma baa gboô ariwo awoôn ara inu ile wa lasiko ti awoôn eeyan yeôn pitu oôwoô woôn.” “Ohun ti mo feô ni ki awoôn oôloôpaa sôisôeô lori eô, kijoôba ba wa da si i nitori mi o feôeô foju sunkun baba mi bayii.” Lati le gboô awijare ori ade ti woôn fi eôsun iwa oôdaran oôhun kan, akoôroyin wa pe Oôba Adeniyi ti i sôe Eletireô tilu Etireô lori eôroô ibanisoôroô, Oôba naa soô pe iroô pata ni woôn pa moô oun. Geôgeô bo sôe soô, “Ko sohun to joô beôeô. Oôba ilu ni mi. Eôni teô eô soô yeôn, oômoô abeô mi lo jeô ninu ilu. Bawo ni mo sôe maa waa ran agbanipa si i.” Njeô bawo loôroô ija ileô sôe jeô, Oôba Adetokunboô dahun, o ni, “Ko sija ileô kankan ti mo n ba a ja. Ilu lo n ba a ja nitori ilu lo nileô, oun lo si gbe ilu loô si kootu.” Geôgeô b’ALAROYE sôe gboô, oôwoô awoôn oôloôpaa ipinleô Ogun ti ba marun-un ninu awoôn ti woôn loôwoô ninu ikoôlu naa, meji ninu woôn, Boôla Adeniyi ati Leke Adeniyi, ni woôn jeô oômoô Oôba Eletireô tilu Etireô. Awoôn meôta yooku ni Yinka Adeniyi to jeô oômoô eôgboôn Eletireô peôlu Foôloôrunsôoô O·peôniyi ati Idowu Risanuwa. Inu ahamoô awoôn oôloôpaa ni woôn wa bayii, nibi ti woôn ti n ran awoôn agbofinro loôwoô ninu iwadii oôran naa. Nigba ti akoôroyin wa pe alukoro awoôn oôloôpaa tipinleô Ogun, DSP Muyiwa Adejoôbi, nipa isôeôleô oôhun, o sôalaye pe woôn ti gbeôjoô naa loô soôdoô igbakeji oôga oôloôpaa eôka keji (Division 2 ) l’Ekoo.
Benzer belgeler
Awon Baale Oke Pata, niluu Ifo so pe Olu Ifo fee da ogun
awako, NURTW, ji
ewure gbe
O ma se o! Awon
oloselu yinbon pa
Kunle l’Edunabon
Lasiko eto imototo,
awon asewo lu olopaa
lalubami l’Akure